Mika 1
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Mika ará Moreṣeti wá ní àkókò ìjọba Jotamu, Ahasi, àti Hesekiah, àwọn ọba Juda nìwọ̀nyí, ìran tí ó rí nípa Samaria àti Jerusalẹmu.
2 Ẹ gbọ́, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn,
    fetísílẹ̀, ìwọ ayé àti gbogbo ohun tó wà níbẹ̀,
kí Olúwa Olódùmarè lè ṣe ẹlẹ́rìí sí yín,
    (A)Olúwa láti inú tẹmpili mímọ́ rẹ̀ wá.
Ìdájọ́ tí o lòdì sí Samaria àti Jerusalẹmu
3 Wò ó! Olúwa ń bọ̀ wá láti ibùgbé rẹ̀;
    yóò sọ̀kalẹ̀, yóò sì tẹ ibi gíga ayé mọ́lẹ̀.
4 Àwọn òkè ńlá yóò sí yọ́ lábẹ́ rẹ̀,
    àwọn Àfonífojì yóò sì pínyà,
bí idà níwájú iná,
    bí omi tí ó ń sàn lọ ni ibi gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́.
5 Nítorí ìré-òfin-kọjá Jakọbu ni gbogbo èyí,
    àti nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli.
Kí ni ìré-òfin-kọjá Jakọbu?
    Ǹjẹ́ Samaria ha kọ?
Kí ni àwọn ibi gíga Juda?
    Ǹjẹ́ Jerusalẹmu ha kọ?
6 “Nítorí náà, èmi yóò ṣe Samaria bí òkìtì lórí pápá,
    bí ibi ti à ń lò fún gbígbin ọgbà àjàrà.
Èmi yóò gbá àwọn òkúta rẹ̀ dànù sínú àfonífojì.
    Èmi yóò sí tú ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ palẹ̀.
7 Gbogbo àwọn ère fínfín rẹ̀ ni a ó fọ́ sí wẹ́wẹ́
    gbogbo àwọn ẹ̀bùn tẹmpili rẹ̀ ni a ó fi iná sun:
    Èmi yóò sì pa gbogbo àwọn òrìṣà rẹ̀ run.
Nítorí tí ó ti kó àwọn ẹ̀bùn rẹ̀ jọ láti inú owó èrè panṣágà,
    gẹ́gẹ́ bí owó èrè panṣágà, wọn yóò sì tún padà sí owó iṣẹ́ panṣágà.”
Ẹkún òun ọfọ̀
8 Nítorí èyí, èmi yóò sì sọkún,
    èmi yóò sì pohùnréré ẹkún:
èmi yóò máa lọ ní ẹsẹ̀ lásán àti ní ìhòhò
    Èmi yóò ké bí akátá,
    èmi yóò sì máa dárò bí àwọn ọmọ ògòǹgò.
9 Nítorí tí ọgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláìlèwòtán;
    ó sì ti wá sí Juda.
Ó sì ti dé ẹnu-bodè àwọn ènìyàn mi,
    àní sí Jerusalẹmu.
10 Ẹ má ṣe sọ ní Gati
    ẹ má ṣe sọkún rárá.
Ní ilẹ̀ Beti-Ofra
    mo yí ara mi nínú eruku.
11 Ẹ kọjá lọ ni ìhòhò àti ni ìtìjú,
    ìwọ tí ó ń gbé ni Ṣafiri.
Àwọn tí ó ń gbé ni Ṣaanani
    kì yóò sì jáde wá.
Beti-Eseli wà nínú ọ̀fọ̀;
    A ó sì gba ààbò rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ yin.
12 Nítorí àwọn tí ó ń gbé ni Marati ń retí ìre,
    Ṣùgbọ́n ibi sọ̀kalẹ̀ ti ọ̀dọ̀ Olúwa wá sí ẹnu-bodè Jerusalẹmu.
13 Ìwọ olùgbé Lakiṣi,
    dì kẹ̀kẹ́ mọ́ ẹranko tí ó yára.
Òun sì ni ìbẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣẹ̀
    sí àwọn ọmọbìnrin Sioni,
    nítorí a rí àìṣedéédéé Israẹli nínú rẹ̀.
14 Nítorí náà ni ìwọ ó ṣe fi ìwé ìkọ̀sílẹ̀
    fún Moreṣeti Gati.
Àwọn ilé Aksibu yóò jẹ́ ẹlẹ́tàn sí àwọn ọba Israẹli.
15 Èmi yóò sì mú àrólé kan wá sórí rẹ ìwọ olùgbé Meraṣa.
    Ẹni tí ó jẹ́ ògo Israẹli
    yóò sì wá sí Adullamu.
16 Fá irun orí rẹ nínú ọ̀fọ̀
    nítorí àwọn ọmọ rẹ aláìlágbára,
sọ ra rẹ̀ di apárí bí ẹyẹ igún,
    nítorí wọn yóò kúrò lọ́dọ̀ rẹ lọ sí ìgbèkùn.
Micah 1
New King James Version
Judgment on Israel and Judah
1 The word of the Lord that came to (A)Micah of Moresheth in the days of (B)Jotham, Ahaz, and Hezekiah, kings of Judah, which he saw concerning Samaria and Jerusalem.
The Coming Judgment on Israel
2 Hear, all you peoples!
Listen, O earth, and all that is in it!
Let the Lord God be a witness against you,
The Lord from (C)His holy temple.
3 For behold, the Lord is coming out of His place;
He will come down
And tread on the high places of the earth.
4 (D)The mountains will melt under Him,
And the valleys will split
Like wax before the fire,
Like waters poured down a steep place.
5 All this is for the transgression of Jacob
And for the sins of the house of Israel.
What is the transgression of Jacob?
Is it not Samaria?
And what are the (E)high places of Judah?
Are they not Jerusalem?
6 “Therefore I will make Samaria (F)a heap of ruins in the field,
Places for planting a vineyard;
I will pour down her stones into the valley,
And I will (G)uncover her foundations.
7 All her carved images shall be beaten to pieces,
And all her (H)pay as a harlot shall be burned with the fire;
All her idols I will lay desolate,
For she gathered it from the pay of a harlot,
And they shall return to the (I)pay of a harlot.”
Mourning for Israel and Judah
8 Therefore I will wail and howl,
I will go stripped and naked;
(J)I will make a wailing like the jackals
And a mourning like the ostriches,
9 For her wounds are incurable.
For (K)it has come to Judah;
It has come to the gate of My people—
To Jerusalem.
10 (L)Tell it not in Gath,
Weep not at all;
In [a]Beth Aphrah
Roll yourself in the dust.
11 Pass by in naked shame, you inhabitant of [b]Shaphir;
The inhabitant of [c]Zaanan does not go out.
Beth Ezel mourns;
Its place to stand is taken away from you.
12 For the inhabitant of [d]Maroth [e]pined for good,
But (M)disaster came down from the Lord
To the gate of Jerusalem.
13 O inhabitant of (N)Lachish,
Harness the chariot to the swift steeds
(She was the beginning of sin to the daughter of Zion),
For the transgressions of Israel were (O)found in you.
14 Therefore you shall (P)give presents to [f]Moresheth Gath;
The houses of (Q)Achzib[g] shall be a lie to the kings of Israel.
15 I will yet bring an heir to you, O inhabitant of (R)Mareshah;[h]
The glory of Israel shall come to (S)Adullam.[i]
16 Make yourself (T)bald and cut off your hair,
Because of your (U)precious children;
Enlarge your baldness like an eagle,
For they shall go from you into (V)captivity.
Footnotes
- Micah 1:10 Lit. House of Dust
- Micah 1:11 Lit. Beautiful
- Micah 1:11 Lit. Going Out
- Micah 1:12 Lit. Bitterness
- Micah 1:12 Lit. was sick
- Micah 1:14 Lit. Possession of Gath
- Micah 1:14 Lit. Lie
- Micah 1:15 Lit. Inheritance
- Micah 1:15 Lit. Refuge
Micah 1
English Standard Version
1 The word of the Lord that came to Micah (A)of Moresheth (B)in the days of Jotham, Ahaz, and Hezekiah, kings of Judah, which he saw (C)concerning (D)Samaria and Jerusalem.
The Coming Destruction
2 (E)Hear, you peoples, all of you;[a]
    (F)pay attention, O earth, and all that is in it,
and (G)let the Lord God be a witness against you,
    (H)the Lord from his holy temple.
3 For behold, (I)the Lord is coming out of (J)his place,
    and will come down and (K)tread upon the high places of the earth.
4 And (L)the mountains will melt under him,
    and the valleys will split open,
like wax before the fire,
    like waters poured down a steep place.
5 All this is for (M)the transgression of Jacob
    and for the sins of the house of Israel.
(N)What is the transgression of Jacob?
    Is it not (O)Samaria?
And what is (P)the high place of Judah?
    Is it not Jerusalem?
6 Therefore I will make (Q)Samaria (R)a heap in the open country,
    a place for planting vineyards,
and I will pour down her stones (S)into the valley
    and (T)uncover her foundations.
7 All (U)her carved images shall be beaten to pieces,
    (V)all her wages shall be burned with fire,
    and all her idols I will lay waste,
for from (W)the fee of a prostitute she gathered them,
    and to the fee of a prostitute they shall return.
8 (X)For this I will lament and wail;
    I will go (Y)stripped and naked;
I will make lamentation (Z)like the jackals,
    and mourning (AA)like the ostriches.
9 (AB)For her wound is incurable,
    and it has come to Judah;
it has reached to the gate of my people,
    to Jerusalem.
10 (AC)Tell it not in (AD)Gath;
    weep not at all;
in Beth-le-aphrah
    (AE)roll yourselves in the dust.
11 Pass on your way,
    inhabitants of Shaphir,
    (AF)in nakedness and shame;
the inhabitants of Zaanan
    do not come out;
the lamentation of Beth-ezel
    shall take away from you its standing place.
12 For the inhabitants of Maroth
    wait anxiously for good,
because disaster has come down (AG)from the Lord
    to the gate of Jerusalem.
13 Harness the steeds to the chariots,
    inhabitants of (AH)Lachish;
it was the beginning of sin
    to the daughter of Zion,
for in you were found
    (AI)the transgressions of Israel.
14 Therefore you shall give parting gifts[b]
    to (AJ)Moresheth-gath;
the houses of (AK)Achzib shall be a deceitful thing
    to the kings of Israel.
15 I will again bring (AL)a conqueror to you,
    inhabitants of (AM)Mareshah;
the glory of Israel
    shall come to (AN)Adullam.
16 (AO)Make yourselves bald and cut off your hair,
    for the children of your delight;
(AP)make yourselves as bald as the eagle,
    for they shall go from you into exile.
Footnotes
- Micah 1:2 Hebrew all of them
- Micah 1:14 Or give dowry
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.
Scripture taken from the New King James Version®. Copyright © 1982 by Thomas Nelson. Used by permission. All rights reserved.
The ESV® Bible (The Holy Bible, English Standard Version®), © 2001 by Crossway, a publishing ministry of Good News Publishers. ESV Text Edition: 2025.

