Font Size
Matiu 12:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Matiu 12:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 Nígbà tí àwọn Farisi rí èyí. Wọ́n wí fún pé, “Wò ó! Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ ń ṣe ohun tí kò bá òfin mu ní ọjọ́ ìsinmi.”
Read full chapter
Johanu 5:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 5:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
9 Lọ́gán, a sì mú ọkùnrin náà láradá, ó sì gbé àkéte rẹ̀, ó sì ń rìn.
Ọjọ́ náà sì jẹ́ ọjọ́ ìsinmi.
Read full chapter
Johanu 7:43
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 7:43
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
43 Bẹ́ẹ̀ ni ìyapa wà láàrín ìjọ ènìyàn nítorí rẹ̀.
Read full chapter
Johanu 10:19
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 10:19
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
19 (A)Nítorí náà ìyapa tún wà láàrín àwọn Júù nítorí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí.
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.