Font Size
Ìṣe àwọn Aposteli 13:39
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ìṣe àwọn Aposteli 13:39
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
39 Nípa rẹ̀ ni a ń dá olúkúlùkù ẹni tí ó gbàgbọ́ láre kúrò nínú ohun gbogbo, tí a kò lè dá yín láre rẹ̀ nínú òfin Mose.
Read full chapter
Romu 5:1
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Romu 5:1
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Àlàáfíà àti ayọ̀
5 (A)Nítorí náà, níwọ̀n ìgbà tí a ti dá wa láre nípa ìgbàgbọ́, àwa ní àlàáfíà lọ́dọ̀ Ọlọ́run nípasẹ̀ Olúwa wa Jesu Kristi.
Read full chapter
Efesu 2:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Efesu 2:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
9 Kì í ṣe nípa àwọn iṣẹ́, kí ẹnikẹ́ni má ba à ṣògo.
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.